a
Mt 2.18
.
Jeremiah 31:15
15
a
Èyí ni ohun tí
Olúwa
wí:
“A gbọ́ ohùn kan ní Rama
tí ń ṣọ̀fọ̀ pẹ̀lú ẹkún kíkorò.
Rakeli ń sọkún àwọn ọmọ rẹ̀;
kò gbà kí wọ́n tu òun nínú,
nítorí àwọn ọmọ rẹ̀ kò sí mọ́.”
Copyright information for
YorBMYO